Ìwádìí ìjìnlẹ̀ lórí àwọn akọni ìbílẹ̀ yorùbá: aláàfin ọ̀yọ́, ọba lamidi ọláyíwolá adeyẹmí gẹ́gẹ́ bí apẹẹrẹ

Um estudo aprofundado dos heróis tradicionais iorubás: Alafin Oyo, Rei Lamidi Olayiwola Adeyiemi como exemplo

Autores/as

Palabras clave:

Aláàfin, Àṣà, Ìṣẹ̀ṣe, Ààbò, Akọni, Ààfin, Yorùbá

Resumen

Nínú àwọn Aláàfin Ọ̀yọ́ mẹ́jẹ̀ẹ̀jọ́ tí wọ́n ti jẹ ní ìlú Ọ̀yọ́ bẹ̀rẹ̀ láti ọdún 1835 sí 2022, Ọba Lamidi Olayiwọla Adeyẹmi III yàtọ̀ gédégbé látàrí ìfẹ́ àìlábàwọ́n tí ó ní sí àṣà àti ìṣẹ̀ṣe Yorùbá, èyí tí ó yà á sọ́tọ̀ tí ó sì ṣe àfihàn-an rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọni nínú àwọn Ọba  tó ti jẹ ní ìlú Ọ̀yọ́ àti ní ilẹ̀ káàárọ̀-oò-jíire, Síbẹ̀, kò tíì sí iṣẹ́ ìwádìí kan pàtàkì tó ṣe àfihàn-an rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí akọni Yorùbá. Èrèdí iṣẹ́ yìí ni láti ṣe ọ̀fíntótó ipa tí Aláàfin Adeyẹmi kẹta kó lórí ìdáàbòbò àti àtúnṣe Ààfin rẹ̀ àti Àṣà òun ìṣẹ̀ṣe Yorùbá lápapọ̀. Èròńgbà wa ni láti; (a) ṣe ìwádìí ọgbọ́n tí Aláàfin dá láti gbé àṣà Yorùbá lárugẹ; àti (b) ṣe àyẹ̀wò ipa tí ó kó láti dáàbòbò àṣà àti ìṣẹ̀ṣe Yorùbá. Iṣẹ́ yìí ṣe àmúlo tíọ́rì aṣèdáàbòbò-àṣà ìbílẹ̀  gẹ́gẹ́ bí atọ́nà béẹ̀ ni a lo ọgbọ́n ìṣèwádìí ìfìwádìí -ṣètúpalẹ̀ -alámùúyẹ ní ìlànà “ó-ṣojúù-mi-kòró” ṣe ọ̀nà ìgbàṣe iṣẹ́. Ì̀wádìí fi gúnlẹ̀ pé, Aláàfin ṣe àyípadà sí ipò Ọba tí ó sì fi bá ìlànà òde òni àti àtijọ́ mu èyí tí ó mú ki ipò náà sì wà ní àìlèfọwọ́rọ́ sẹ́yìn di òní bí ipò òṣèlú tilẹ̀ ń yípadà. Iṣẹ́ yìí fi gúnlẹ̀ wípé Aláàfin ṣì dúró bíi ààmù fún àṣà àti ìṣẹ̀ṣe Yorùbá.  Iwádìí dá a lábàá pé, kí àjọṣe wà láàrin Ìjóba àti àwọn ọba lati ríi pé ààbò tó péye wà fún àṣà àti ìṣẹ̀ṣe àti ìgbélárugẹ̀ méjèèjì.

********

Entre os oito Alaafins de Oyo que governaram Oyo de 1835 a 2022, o Oba Lamidi Olayiwola Adeyemi III destaca-se pelo seu amor inabalável pela cultura e pelas tradições iorubás; tal característica o distinguiu e o consagrou como um herói entre os reis que governaram Oyo e o restante do país. No entanto, não houve trabalhos de pesquisa significativos que o tenham estabelecido formalmente como um herói iorubá. O objetivo deste trabalho é examinar o papel desempenhado pelo Alaafin Adeyemi III na preservação e restauração de seu palácio, bem como da cultura e das tradições iorubás em geral. Pretendemos: (a) investigar a estratégia criada pelo Alaafin para promover a cultura iorubá; e (b) examinar o papel que ele desempenhou na proteção da cultura e das práticas iorubás. Este estudo utiliza a teoria da proteção da cultura tradicional como diretriz e emprega o método de pesquisa *alamuüyü* (investigação-análise), fundamentado no princípio de "*o-sōjuù-mi-koro*", como metodologia de trabalho. A pesquisa concluiu que o Alaafin transformou a posição do rei, tornando-a compatível tanto com princípios modernos quanto antigos; isso conferiu à função uma perenidade que perdura até hoje, a despeito das mudanças no cenário político. O trabalho conclui que o Alaafin permanece como um pilar da cultura e das práticas iorubás. A pesquisa demonstrou a necessidade de uma relação entre o governo e os reis para assegurar a proteção adequada dos costumes e práticas, bem como a sua promoção.

 

Descargas

Los datos de descargas todavía no están disponibles.

Biografía del autor/a

Roheemat Olabimpe ADEYEMI , University of Ilọrin - Nigeria

is a Lecturer at the University of Arts, University of Ilọrin, Department of Linguistics and Nigerian Languages. Her research focuses on Yoruba oral and written literature, exploring topics on Orature, Stylistics and Linguistics. She continues to contribute to the field of Yoruba studies, investigating language, culture, and conflict management.

Citas

Adeyemi, R. O. (2025). A speech act study of Rárà Aláàfin Ọ̀yọ́. Unpublished Ph.D. thesis, University of Ilorin, Nigeria.

Adeyemi, R.O. (2008). Iwádìí ìjìnlẹ̀ lórí oríkì -orílẹ̀ àwọn Aláàfin Ọ̀yọ́ (1837-2008). M.A project. Department of Linguistics and Nigerian Languages, University of Ilorin, Ilorin. Nigeria.

Akinjogbin, I. A. (1967). Dahomey and its neighbours, 1708–1818. Cambridge: Cambridge University Press.

Finnegan, R. (2012). Oral literature in Africa (Open access ed.). Cambridge, England: Open Book Publishers.

Johnson, S. (1921). The history of the Yorubas. Lagos, Nigeria: CMS Bookshops.

Law, R. (1977). The Oyo Empire c.1600–1836: A West African imperialism in the era of the Atlantic slave trade. Oxford, England: Clarendon Press.

Mafeje, A. (2003). The ideology of tribalism. Journal of African Cultural Studies, 16(1), 25–36.

Mbembe, A. (2001). On the postcolony. Berkeley, CA: University of California Press.

Ngũgĩ wa Thiong’o. (1986). Decolonising the mind: The politics of language in African literature. London: James Currey.

Nyamnjoh, F. B. (2016). Rhodes Must Fall: Nibbling at resilient colonialism in South Africa. Bamenda: Langaa Research.

Oyediran, R.O. (2002). Ipa, ipò àti ojúṣe àwọn ọba nílẹ̀ Yorùbá: Aláàfin Ọ̀yọ́ gẹ́gẹ́ bí àpẹẹrẹ. B.A. project, Department of Linguistics &Nigerian Languages, University of Ilorin, Ilorin.

Ranger, T. (1983). The invention of tradition in colonial Africa. In E. Hobsbawm & T. Ranger (Eds.), The invention of tradition (pp. 211–262). Cambridge, England: Cambridge University Press.

Rank, O., Raglan, L., & Dundes, A. (1990). In quest of the hero. Princeton, NJ: Princeton University Press.

Shils, E. (1981). Tradition. Chicago: University of Chicago Press.

UNESCO. (2003). Convention for the safeguarding of intangible cultural heritage. Paris: UNESCO.

Publicado

27-08-2026

Cómo citar

ADEYEMI , R. O. (2026). Ìwádìí ìjìnlẹ̀ lórí àwọn akọni ìbílẹ̀ yorùbá: aláàfin ọ̀yọ́, ọba lamidi ọláyíwolá adeyẹmí gẹ́gẹ́ bí apẹẹrẹ: Um estudo aprofundado dos heróis tradicionais iorubás: Alafin Oyo, Rei Lamidi Olayiwola Adeyiemi como exemplo. NJINGA&SEPÉ: evista nternacional e ulturas, Línguas fricanas rasileiras, 6(Especial II), 141–156. ecuperado a partir de https://revistas.unilab.edu.br/njingaesape/article/view/2910