Àgbéyẹ̀wò Ìjẹyọ Àwọn Akínkanjú Nínú Onírúurú Oríkì Yorùbá
Uma análise da aparição de heróis em diversos poemas iorubás
Palabras clave:
Akínkanjú, Apohùn, Ìtúntànrọ, Lítíréṣọ̀ Àbáláyé, OríkìResumen
Onírúurú nǹkan ló ṣodo sínú lítíréṣọ̀ àbáláyé Yorùbá eyí tí oríkì jẹ́ ọ̀kan gbòógì nínú wọn. Bí a ṣe ní oríkì orílẹ̀ ni oríkì ìlú, oríkì bọ̀rọ̀kìnní, oríkì oúnjẹ, oríkì ẹranko, bẹ́ẹ̀ oríkì àmútọ̀runwá náà wà. Kókó pàtàkì tí iṣẹ́ àpilẹ̀kọ yìí gùn lé ni àgbéyẹ̀wò àṣàyàn àwọn akínkanjú ọmọ Yorúbá bí wọ́n ṣe jẹyọ nínú àṣàyàn oríkì orílẹ̀ bíi Oníkòyí, Òpómúléró, Àwórì, Olufẹ̀ àti àṣàyàn oríkì ìlú bíi Ìbàdàn, Ìlọrin, Ẹdẹ, Ògbómọ̀ṣọ́ àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ. Oríkì bọ̀rọ̀kìnní náà kò gbẹ́yìn lára àwọn oríkì tí a ṣàmúlò fún àkànṣe ìwádìí yìí. Ìlànà ìwádìí ni ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú àwọn òjìnmí apohùn ìbílẹ̀ àtí àyẹ̀wò onírúurú àwọn ìwé tó wà lórí oríkì Yorùbá. Tíọ́rí tí a ṣàmúlò fún ọ̀ríkínniwín àtúpalẹ̀ iṣẹ́ yìí ni Tíọ́rì Ìmọ̀ Ọnà-Ìsọ̀tàn (Narratological Theory) àti Tíọ́rì Ìbára-gbé-pọ̀ (Sociological Theory). Iṣẹ yìí fìdí rẹ̀ múlẹ̀ pé nípasẹ̀ ṣiṣe ìwádìí ìjìnlẹ̀ nínú onírúurú oríkì Yorùbá, oríṣiríṣi àwọn akínkanjú-kùnrin àti akínkanjú-bìnrin ló máa ń jẹ jáde lórí ipa ribiribi tí wọ́n ti kó fún ìtẹ̀lúdó, ìjìjàgbara fún ìlú kóówá wọn, ìtàn ìṣẹ̀dálẹ̀ wọn, ìtànkálẹ̀ ìran wọn, ọrọ̀-ajé wọn, ètò-ìṣèlú wọn àti onírúuru kókó ajẹmọ́-ìdàgbàsókè lóríṣiríṣi. Nítorí náà, àwọn oríkì Yorùbá kún fọ́fọ́ọ́fọ́ fún òkodoro ọ̀rọ̀ nípa ìtàn àtijọ́ tí ó wúlò fún mímọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdí abájọ àti ìtúntànrọ lóde òní nípa onírúuru àwọn akínkanjú ọmọ Yorùbá.
*******
A literatura tradicional iorubá abrange diversas formas de expressão, entre as quais se destaca a poesia. Assim como existe a poesia nacional, há também a poesia urbana, a poesia folclórica, bem como poesias que versam sobre alimentação, animais e o divino. O objetivo central deste artigo é examinar a figura dos heróis iorubás conforme surgem tanto na poesia nacional — como Onikoy, Opomulero, Awori e Olufe — quanto na poesia local, associada a cidades como Ibadan, Ilorin, Ede e Ogbomoso, entre outras. A poesia folclórica também figura entre os gêneros poéticos analisados neste estudo. A metodologia de pesquisa baseia-se em entrevistas com estudiosos locais e na revisão de diversas obras sobre a poesia iorubá. As teorias empregadas na análise são a Teoria Narratológica e a Teoria Sociológica. O estudo demonstra que, por meio de uma análise aprofundada de diversos poemas iorubás, revelam-se homens e mulheres heroicos e suas imensas contribuições para o desenvolvimento e a defesa da terra natal, bem como para a história de sua criação, a expansão de suas linhagens, a economia, o sistema político e outros aspectos relacionados ao desenvolvimento. Portanto, a poesia iorubá é rica em detalhes históricos valiosos para a compreensão das razões e das narrativas contemporâneas acerca de diversos heróis iorubás.
Descargas
Citas
Adéọ̀ṣun, H.O. (2025). Oríṣìíríṣìí Ewì Yorùbá. Nínú Àkọ̀tun Ìmọ̀ Nínú Gírámà, Lítíréṣọ̀ àti Àṣà Yorùbá (Ní Ìlànà CCMAS). Adéyẹmí Ọlálérè, adéọ̀ṣun Hezekiah Olúfẹ́mi àtiArókoyọ̀ Bọ́láńlé Elizabeth (Àwọn Olóòtú), pp. 380-381. Department of Linguistics and Nigerian languages, University of Ìlọrin, Ìlọrin.
Adésọjí, A.O. (2004), “Globalisation and The Challenges of Historical Reconstruction in Nigeria” In: Locating The Local in the Global: Voices on a Globalised Nigeria, : 64-71. (ed)
Ajíbádé, G.O. (2005a), “Multifaces of Word in Yorùbá Orature.” Journal of Language and Literature 4(1): 20-39.
Akínyẹmí, A. (2004), Yorùbá Royal Poetry. A Socio-historical Exposition and Annotated Translation. Bayreuth: Rosch Buch.
Babalọlá, A. (1981). Àwọn Oríkì Bọ̀rọ̀kìnní. Ìbàdàn: Rosprint Industrial Press Limited.
Babalọlá, A. (2000), Àwọn Oríkì Orílẹ̀ Mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n. Lagos: Longman Nigeria Plc.
Bákàrè, A. (2007), “Ìtúpalẹ̀ Ewì Ọdún Ọba ni àwọn ìlú Ajórúkọmọ́-Òwu.” M.A. Thesis, Department of African Languages and Literatures, Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ University, Ile-Ifẹ̀
Barber, K. (1979), “Sociology of Yorùbá Oral Literature: Oríkì Òkukù”. Seminar paper, Department of African Languages and Literatures, University of Ifẹ̀, Ilé-Ifẹ̀.
Barber, K. (1991), I Could Speak Until Tomorrow: Oríkì, Women and the Past in a Yorùbá Town. Edinburgh: Edinburgh University Press.
Barber, K. (2003), “Text and Performance in Africa” in: Bulletin of the School of Oriental and African Studies. 66(3): 324-33.
Barry, P. (2002), Beginning Theory. UK: Manchester University Press.
Caudwell, C. (1977), Illusion and Reality. London: Lawrence and Wishart.
Fágúnwà, D.O (2005). Ògbójú Ọdẹ Nínú Igbó Irúnmọlẹ̀. Ìbàdàn: Nelson Publishers Limited.
Johnson, S. (1922) The History of the Yorubas. Lagos: C.M.S. Bookshops.
Ládélé, T.A.A. àti Fáníyì, J.O.O. (1979), Ẹkún Ìyàwó. Lagos: Longman.
Ládélé, T.A.A, Awórìndé, I.A., Mustapha, O., Ọládàpọ̀ O., àti Oyèrìndé, O. (2006) Àkójọpọ̀ Ìwádìí Ìjìnlẹ̀ Àṣà Yorùbá. Ìbàdàn: Macmillan Nigeria Publishers Limited.
Láṣebìkan, E.L. (1958), Ìjìnlẹ̀ Ohùn Ẹnu Yorùbá, Àkójọ Kínní. Ìbàdàn: Government Printers.
Lawanson, O. (2010). Àwọn Oríkì Mẹ́ta Ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀. Lagos : Afbax Communications
Ògúnrẹ̀mí, Ọ. (2012). Oríkì Orílẹ̀ Àti T’ogójì Ìlú Nílẹ̀ Yorùbá. Ilé-Ifẹ̀: Matolog Nigeria Enterprises.
Ògúnṣínà, B. (1987), “The Sociology of the Yorùbá Novels: A Study of Isaac Thomas, D.O. Fágúnwà and Ọládẹ̀jọ Òkédìjí”, Ph.D. Thesis, University of Ibadan, Ìbàdàn.
Ọlátúnjí, O. (1984), Features of Yorùbá Oral Poetry. Ìbàdàn: University Press Limited.
Ọmọlọlá, B. (2016). Hero, Heroine and Heroism. In Encyclopedia of the Yorùbá. Fálọlá Tóyìn, Akínyẹmí Akíntúndé (Ed). Pp.151-152. Bloomington & Indianapolis: Indiana University Press.
Ọ̀pẹ́fèyítìmí, A. (1997), Tíọ́rì àti Ìṣọwọ́lòèdè. Òsogbo: Tánímẹ̀hìn-ọ̀la Press.
Descargas
Publicado
Cómo citar
Número
Sección
Licencia
Derechos de autor 2026 NJINGA&SEPÉ: Revista Internacional de Culturas, Línguas Africanas e Brasileiras

Esta obra está bajo una licencia internacional Creative Commons Atribución-NoComercial-SinDerivadas 4.0.
Los autores que publican en esta revista aceptan los siguientes términos:
Los autores mantienen los derechos de autor y otorgan a la revista el derecho a la primera publicación, siendo el trabajo simultáneamente licenciado bajo la Licencia de Atribución Creative Commons, que permite compartir el trabajo con reconocimiento de la autoría del trabajo y la publicación inicial en esta revista.
Se autoriza a los autores a asumir contratos adicionales por separado, para la distribución no exclusiva de la versión del trabajo publicado en esta revista (p. Ej., Publicación en repositorio institucional o como capítulo de libro), con reconocimiento de autoría y publicación inicial en esta revista.
Se permite y se anima a los autores a publicar y distribuir su trabajo en línea (por ejemplo, en repositorios institucionales o en su página personal) en cualquier momento antes o durante el proceso editorial, ya que esto puede generar cambios productivos, así como aumentar el impacto y cita del trabajo publicado (Ver El efecto del acceso abierto).