Àfihàn ẹwúrù gẹ́gẹ́ bi akọnibìnrin ìlú mòro: ẹ̀rí láti inú lítíréṣọ̀ alohùn yorùbá

The portrayal of ẹwúrù as a heroine in mòro: references from yorùbá oral literature

Autores

  • Raphael Ayodeji ADESUYAN Adéyẹmí Federal University of Education, Oǹdó, Oǹdó State, Nigeria, https://orcid.org/0009-0006-2088-9136
  • Julius Oyewole ADEBOYE Adeyemi Federal University of Education -Nigeria

Palavras-chave:

Òrìṣà Ewúrù, Akọnibìnrin, Lítírẹ́ṣọ̀ Alohùn, Tíọ́rì Àbùdá-Akọni, Ìlú Mòro

Resumo

Iṣẹ́ ìwádìí yìí ṣe àgbéyẹ̀wò àfihàn Ewúrù gẹ́gẹ́ bí akọnibìnrin nípasẹ̀ lítírẹ́ṣọ̀ àlọ́hùn Yorùbá. Àkíyèsí fi hàn pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ ìwádìí tí ó ti wà lórí lítíréṣọ̀ alọ́hùn Yorùbá ni ó rọ̀ mọ́ akọni ọkùnrin, èyí tí ó mú kí ojúṣe àti agbára àwọn akọni obìnrin nínú ìtàn ìwáṣẹ̀ dín kù. Àfojúsùn wádìí yìí ni láti dí àlàfo yìí nípa ṣíṣe àyẹ̀wò Òrìṣà Ẹwúrù gẹ́gẹ́ bí akọnibìnrin ní ìlú Mòro láti túbọ̀ wo ipò akọnibìnrin nínú ìtàn àti àṣà Yorùbá. Ìlànà ìṣẹ̀wádìí méjì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni a lò fún iṣẹ́ yìí: àkọ́kọ́ ni ṣíṣe àkójọpọ̀ ewì Òrìṣà Ewúrù tí ó tọ́ka sí ìwà akọnibìnrin tí Ewúrù hù, èyí tí ó fi di akọni òrìṣà nígbà tí ó kú tán. Bákan náà ni a tún ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò fún àwọn agbátẹrù Òrìṣà Ewúrù (ọkùnrin àti obìnrin mẹ́sàn-án) ní ìlú Mòro. Ìlànà ìṣẹ̀wádìí kejì tí a lò ni ṣíṣe àmúlò àwọn ìwé tí ó wúlò fún iṣẹ́ yìí; bíi àwọn àpilẹ̀kọ, ìwé, àti àwọn ìwé orí ẹ̀rọ ayélujára. Ìtúpalẹ̀ àwọn àkójọpọ̀ wọ̀nyí ni a ṣe pẹ̀lú Tíọ́rì Àbùdá-Akọni (Archetypal Criticism). Àbájáde ìwádìí yìí fi hàn pé Ewúrù kì í ṣe òrìṣà lásán, bí kò ṣe akọnibìnrin tí ó lo agbára àbínibí àti ti ẹ̀mí rẹ̀ láti pèsè ààbò, àlàáfíà, àti ọmọ fún àwùjọ Mòro nínú ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú Láòbú nígbà ayé wọn. Iṣẹ́ yìí fi kún ìmọ̀ nínú lítírẹ́ṣọ̀ àlọ́hùn Yorùbá nípa títọ́ka sí bí obìnrin ṣe ń jẹ́ òpómúléró ìdàgbàsókè àti ìṣọ̀kan nínú ìtàn ìwásẹ̀ ilẹ̀ Adúláwọ̀.

******* 

This research paper examines the portrayal of Ewúrù as a heroine in Yorùbá oral literature. Observation shows that most studies on heroism in Yorùbá literature predominantly focus on male heroes, thereby overlooking the status and power of mythic heroines like Ewúrù; this is the academic lacuna that this study intends to fill. Two distinct research methodologies were adopted for this study: the first involves the collection of Ewúrù deity poetry that highlights the heroic deeds she performed, which elevated her to a revered hero-deity after her transition. Similarly, in-depth interviews were conducted with nine custodians of the Ewúrù deity (both male and female) in Mòro town. The second research methodology involves the utilization of relevant literature, including journal articles, books, and internet resources. The collected data were transcribed and analyzed using Archetypal Criticism as the theoretical framework. The findings of this study reveal that Ewúrù is not merely a deity, but a heroine who deployed her innate and spiritual powers to provide security, peace, and children for the Mòro community through her covenant with Láòbú. This study contributes to the body of knowledge in Yorùbá oral literature by highlighting how women serve as pillars of development and unity in African etiological narratives.

Downloads

Não há dados estatísticos.

Biografia do Autor

Raphael Ayodeji ADESUYAN, Adéyẹmí Federal University of Education, Oǹdó, Oǹdó State, Nigeria,

is a Professor of Yorùbá Language and Literature at Adeyemi Federal University of Education, Ondo State, Nigeria. He attended Obafemi Awolowo University, Ile-Ife, Osun State, Nigeria, from where he obtained his B.A., M.A. and Ph.D, Yorùbá Language and Literature. He also attended University of Ilorin, Ilorin, Kwara State, Nigeria, from where he obtained his M.A. Yorùbá Language. His teaching, research work and publications focus on Yorùbá language and literature with specialization in syntax and dialectology. He has authored two books and published over forty papers in leading books and journals in Nigeria and abroad. He also served as Chief Editor on the editorial boards of several books and journals. He has attended national and international conferences and presented papers. He is an active member of several professional associations. His current research work focuses on function words in South-East Yorùbá dialects.

Julius Oyewole ADEBOYE , Adeyemi Federal University of Education -Nigeria

Iṣẹ́ ìwádìí yìí ṣe àgbéyẹ̀wò àfihàn Ewúrù gẹ́gẹ́ bí akọnibìnrin nípasẹ̀ lítírẹ́ṣọ̀ àlọ́hùn Yorùbá. Àkíyèsí fi hàn pé ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ ìwádìí tí ó ti wà lórí lítíréṣọ̀ alọ́hùn Yorùbá ni ó rọ̀ mọ́ akọni ọkùnrin, èyí tí ó mú kí ojúṣe àti agbára àwọn akọni obìnrin nínú ìtàn ìwáṣẹ̀ dín kù. Àfojúsùn wádìí yìí ni láti dí àlàfo yìí nípa ṣíṣe àyẹ̀wò Òrìṣà Ẹwúrù gẹ́gẹ́ bí akọnibìnrin ní ìlú Mòro láti túbọ̀ wo ipò akọnibìnrin nínú ìtàn àti àṣà Yorùbá. Ìlànà ìṣẹ̀wádìí méjì ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ni a lò fún iṣẹ́ yìí: àkọ́kọ́ ni ṣíṣe àkójọpọ̀ ewì Òrìṣà Ewúrù tí ó tọ́ka sí ìwà akọnibìnrin tí Ewúrù hù, èyí tí ó fi di akọni òrìṣà nígbà tí ó kú tán. Bákan náà ni a tún ṣe ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò fún àwọn agbátẹrù Òrìṣà Ewúrù (ọkùnrin àti obìnrin mẹ́sàn-án) ní ìlú Mòro. Ìlànà ìṣẹ̀wádìí kejì tí a lò ni ṣíṣe àmúlò àwọn ìwé tí ó wúlò fún iṣẹ́ yìí; bíi àwọn àpilẹ̀kọ, ìwé, àti àwọn ìwé orí ẹ̀rọ ayélujára. Ìtúpalẹ̀ àwọn àkójọpọ̀ wọ̀nyí ni a ṣe pẹ̀lú Tíọ́rì Àbùdá-Akọni (Archetypal Criticism). Àbájáde ìwádìí yìí fi hàn pé Ewúrù kì í ṣe òrìṣà lásán, bí kò ṣe akọnibìnrin tí ó lo agbára àbínibí àti ti ẹ̀mí rẹ̀ láti pèsè ààbò, àlàáfíà, àti ọmọ fún àwùjọ Mòro nínú ìbáṣepọ̀ rẹ̀ pẹ̀lú Láòbú nígbà ayé wọn. Iṣẹ́ yìí fi kún ìmọ̀ nínú lítírẹ́ṣọ̀ àlọ́hùn Yorùbá nípa títọ́ka sí bí obìnrin ṣe ń jẹ́ òpómúléró ìdàgbàsókè àti ìṣọ̀kan nínú ìtàn ìwásẹ̀ ilẹ̀ Adúláwọ̀.

******* 

Esta pesquisa examina a representação de Ewuru como heroína na literatura oral iorubá. Vale ressaltar que a maior parte das pesquisas sobre a literatura oral iorubá tem se concentrado em heróis masculinos, o que acabou por diminuir o papel e o poder das heroínas na história e na narrativa. O objetivo deste estudo é preencher essa lacuna analisando a Deusa Ewuru como heroína na cidade de Mòro, a fim de aprofundar a compreensão sobre o papel da heroína na história e na cultura iorubá. Dois métodos de pesquisa distintos foram empregados neste trabalho: o primeiro consistiu em reunir poemas sobre a Deusa Ewuru que descrevem os feitos heroicos realizados por ela — ações que a elevaram ao status de deusa heroína após sua morte. Paralelamente, foram realizadas entrevistas com devotos da Deusa Ewuru (nove homens e nove mulheres) na cidade de Mòro. A segunda estratégia de pesquisa envolveu a utilização de literatura pertinente ao tema, incluindo artigos, livros e recursos online. A análise desse material foi realizada à luz da Crítica Arquetípica. Os resultados da pesquisa revelam que Ewuru não é apenas uma deusa, mas uma heroína que empregou seus poderes naturais e espirituais para proporcionar proteção, paz e descendência à comunidade de Mòro, no contexto de sua relação com Laobú àquela época. Este trabalho contribui para o conhecimento da literatura oral iorubá ao destacar o papel das mulheres como força motriz do desenvolvimento e da unidade na história do continente africano.

Referências

Adéoyè, C. L. (1985). Ìgbàgbọ́ àti ẹ̀sìn Yorùbá. Evans Brothers Nigeria Publishers Limited.

Campbell, J. (1949). The hero with a thousand faces. Pantheon Books.

Deyab, M. C. (2023). Womanism, definition and history [Manuscript submitted for publication]. Department of English, Faculty of Arts, Minia University.

Fátùrótì, O. R. (2019). Ìgbàgbọ́ àwọn Yorùbá nínú Olódùmarè àti ìṣẹ̀dá ènìyàn. Nínú R. Adéṣuyan, S. M. Rájí, M. A. Fasehun, & I. F. Òjó (ol.), Ẹ̀kọ́ èdè, àṣà àti lítíréṣọ̀ Yorùbá (ojú-ìwé 148-169). Masterprint Publishers.

Faturoti, O. R. (2019). Litireso alohun ati esin ibile: Itupale ipo awon orisa ninu asa Yorùbá. Osun Journal of Yorùbá Studies, 4(2), 25–38.

Frye, N. (1957). Anatomy of criticism: Four essays. Princeton University Press.

Guerin, W. L., Labor, E., Morgan, L., Reesman, J. C., & Willingham, J. R. (2005). A handbook of critical approaches to literature (5th ed.). Oxford University Press.

Mbiti, J. S. (1990). African religions & philosophy (2nd ed.). Heinemann.

Ọládélé, B. (1986). Àwọn oríkì orílẹ̀ Mòro [Àpilẹ̀kọ fún gbígba oyè ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ àkọ́kọ́]. University of Ilorin.

Reeve, C. (1990). The complete Tutenkhanmun: The king,the tomb, the royal treasure. Random House.

Downloads

Publicado

27-08-2026

Como Citar

ADESUYAN, R. A., & ADEBOYE , J. O. (2026). Àfihàn ẹwúrù gẹ́gẹ́ bi akọnibìnrin ìlú mòro: ẹ̀rí láti inú lítíréṣọ̀ alohùn yorùbá: The portrayal of ẹwúrù as a heroine in mòro: references from yorùbá oral literature. JINGA SEPÉ: evista nternacional e ulturas, Línguas fricanas rasileiras (ISSN: 2764-1244), 6(Especial II), 217–231. ecuperado de https://revistas.unilab.edu.br/njingaesape/article/view/2914